Ife-itumo-loju: Wiwa Ord-iperi Fun Arun Kokoro-Apa-Soja-Ara (KASA) ati Ebola

No Thumbnail Available

Date

2021

Journal Title

Journal ISSN

Volume Title

Publisher

Library Press @ UF

Abstract

Ọ̀pọ̀ ọ̀nà ni àwọn onímọ̀ ti dá lábàá fún ṣíṣe àwárí tàbí ìṣèdá ọ̀rọ̀-ìpẹ̀rí nínú èdè Yorùbá, lára wọn ni ìṣàlàyé, ìhùn-prọ́-pọ̀, ìfìṣàpẹẹrẹ, ìlọ́wẹ̀, ọ̀rọ̀-àyálọ̀, ìfẹ́-ìtumọ̀-lójú àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Ìfẹ́-ìtumọ̀-lójú ni ó jẹ́ ìwádìí yìí lógún nípa wíwá prọ́-ìpẹ̀rí fún àrùn Kókóró-Àpá-Sọjà-Àrà (KASA) àti Ebola. A ṣe àgbéyẹ̀wò 1572 ọ̀rọ̀ tí Yusuff, Adétúnjí àti Odòjé (2017) jẹ́ olóòtú fìlìmù, a sì fa àwọn tí wọ́n fẹ́ ìtumọ̀ wọn lójú yọ fún iṣẹ́ ìwádìí tí a ṣe. A ṣàwárí pé oríṣìíríṣìí mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni irú àwọn ọ̀rọ̀ yìí; kò sì sí ìyọnu láti ní òye ìtumọ̀ tuntun tí a wá wọ àwọn ọ̀rọ̀ náà lórí wọn. Ó tilẹ̀ mú ìtumọ̀ gbé tán bá àwọn ọ̀rọ̀ tuntun tí a lò wọ́n fún.

Description

In: Yoruba Studies Review 4(1), pp. 139-146

Keywords

Kokoro-Apa-Soja-Ara (KASA), Ebola

Citation

Collections

Endorsement

Review

Supplemented By

Referenced By